النّاس

تفسير سورة النّاس

الترجمة اليورباوية

Yorùbá

الترجمة اليورباوية

ترجمة معاني القرآن الكريم للغة اليوربا ترجمها الشيخ أبو رحيمة ميكائيل أيكوييني عام الطبعة 1432هـ .

﴿بِسْمِ اللَّهِ الرَّحْمَٰنِ الرَّحِيمِ قُلْ أَعُوذُ بِرَبِّ النَّاسِ﴾

Sọ pé: "Mo sá di Olúwa àwọn ènìyàn,

﴿مَلِكِ النَّاسِ﴾

Ọba àwọn ènìyàn,

﴿إِلَٰهِ النَّاسِ﴾

Ọlọ́hun àwọn ènìyàn,

﴿مِنْ شَرِّ الْوَسْوَاسِ الْخَنَّاسِ﴾

níbi aburú (Èṣù) oníròyíròyí, olùsásẹ́yìn (fún ẹni t’ó bá dárúkọ Allāh).

﴿الَّذِي يُوَسْوِسُ فِي صُدُورِ النَّاسِ﴾

(Èṣù ni) ẹni tí ó ń kó ròyíròyí sínú àwọn ọkàn ènìyàn.

﴿مِنَ الْجِنَّةِ وَالنَّاسِ﴾

(Èṣù náà) wà nínú àlùjànnú àti ènìyàn.

الترجمات والتفاسير لهذه السورة: